Wildebeest analysis examples for:   yor-yor   Ọ    February 25, 2023 at 01:36    Script wb_pprint_html.py   by Ulf Hermjakob

1  GEN 1:1  Ní ìbẹ̀rẹ̀ ohun gbogbo ĺrun àwn ̀run àti ayé.
2  GEN 1:2  Ayé sì wà ní rúdurùdu, ó sì ṣófo, òkùnkùn sì wà lójú ibú omi, Ẹ̀mí ĺrun sì ń rábàbà lójú omi.
3  GEN 1:3  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí ìḿlẹ̀ kí ó wà,” ìḿlẹ̀ sì wà.
4  GEN 1:4  ĺrun rí i pé ìḿlẹ̀ náà dára, ó sì ya ìḿlẹ̀ náà śt̀ kúrò lára òkùnkùn.
5  GEN 1:5  ĺrun sì pe ìḿlẹ̀ náà ní̀sán,” àti òkùnkùn ní “òru.” Àṣálẹ́ àti òwúr̀ sì jẹ́ j́ kìn-ín-ní.
6  GEN 1:6  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí òfúrufú kí ó wà ní àárín àwn omi, láti pààlà sí àárín àwn omi.”
7  GEN 1:7  ĺrun sì dá òfúrufú láti ya omi tí ó wà ní òkè òfúrufú kúrò lára omi tí ó wà ní orí ilẹ̀. Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
8  GEN 1:8  ĺrun sì pe òfúrufú ní̀run.” Àṣálẹ́ àti òwúr̀ sì jẹ́ j́ kejì.
9  GEN 1:9  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí omi abẹ́ ̀run ẃ pap̀ sí ojú kan, kí ilẹ̀ gbígbẹ sì farahàn.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
10  GEN 1:10  ĺrun sì pe ilẹ̀ gbígbẹ náà ní “ilẹ̀,” àti àpap̀ omi ní “òkun.” ĺrun sì rí i wí pé ó dára.
11  GEN 1:11  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó hu ̀gbìn: ewéko ti yóò máa mú èso wá àti igi tí yóò máa so èso ní irú tirẹ̀, tí ó ní irúgbìn nínú.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
12  GEN 1:12  Ilẹ̀ sì hù ̀gbìn: ewéko tí ó ń so èso ní irú tirẹ̀, àti igi tí ń so èso, tí ó ní irúgbìn nínú ní irú tirẹ̀. ĺrun sì ri pé ó dára.
14  GEN 1:14  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí ìḿlẹ̀ kí ó wà ní ojú ̀run, láti pààlà sí àárín ̀sán àti òru, kí wn ó sì máa wà fún àmì láti m àwn àsìkò, àti àwn j́ àti àwn dún.
16  GEN 1:16  ĺrun ìḿlẹ̀ ńlá ńlá méjì, ìḿlẹ̀ tí ó tóbi láti ṣe àkóso ̀sán àti ìḿlẹ̀ tí ó kéré láti ṣe àkóso òru. Ó sì dá àwn ìràẁ pẹ̀lú.
17  GEN 1:17  ĺrun sì ṣe ẃn ĺj̀ sí ojú ̀run láti máa tan ìḿlẹ̀ si orí ilẹ̀,
18  GEN 1:18  láti ṣàkóso ̀sán àti òru àti láti pààlà sí àárín ìḿlẹ̀ àti òkùnkùn. ĺrun sì rí i pé ó dára.
20  GEN 1:20  ĺrun sì wí pé, “Jẹ́ kí omi kí ó kún fún àwn ohun alààyè, kí àwn ẹyẹ kí ó sì máa fò ní òfúrufú.”
21  GEN 1:21  Nítorí náà ĺrun àwn ẹ̀dá alààyè ńlá ńlá sí inú òkun, àwn ohun ẹlẹ́mìí àti àwn ohun tí ń rìn ní onírúurú tiwn, àti àwn ẹyẹ abìyẹ́ ní onírúurú tiwn. ĺrun sì rí i pé ó dára.
22  GEN 1:22  ĺrun súre fún wn, ó sì wí pé, “Ẹ máa bí sí i, ẹ sì máa p̀ sí i, ẹ kún inú omi òkun, kí àwn ẹyẹ náà sì máa p̀ sí i ní orí ilẹ̀.”
24  GEN 1:24  ĺrun sì wí pé, “Kí ilẹ̀ kí ó mú ohun alààyè jáde ní onírúurú wn: ẹran ̀sìn, àwn ohun afàyàfà àti àwn ẹran inú igbó, ̀k̀̀kan ní irú tirẹ̀.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
25  GEN 1:25  ĺrun sì dá ẹranko inú igbó àti ẹran ̀sìn gbogbo ní irú tirẹ̀ àti gbogbo ohun alààyè tí ń rìn ní ilẹ̀ ní irú tirẹ̀. ĺrun sì rí i pé ó dára.
26  GEN 1:26  Lẹ́yìn náà ni ĺrun wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a dá ènìyàn ní àwòrán ara wa, gẹ́gẹ́ bí àwa ti rí, kí wn kí ó jẹ ba lórí ẹja òkun, ẹyẹ ojú ̀run, ẹran ̀sìn, gbogbo ilẹ̀ àti lórí ohun gbogbo tí ń rìn lórí ilẹ̀.”
27  GEN 1:27  Nítorí náà, ĺrun dá ènìyàn ní àwòrán ara rẹ̀, ní àwòrán ĺrun ni ó dá a, ak àti abo ni ó dá wn.
28  GEN 1:28  ĺrun sì súre fún wn, ĺrun sì wí fún wn pé, “Ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì máa p̀ sí i, kí ẹ sì gbilẹ̀, kí ẹ ṣe ìkápá ayé. Ẹ ṣe àkóso àwn ẹja inú òkun, ẹyẹ ojú ̀run àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó ń rìn ní orí ilẹ̀.”
29  GEN 1:29  Nígbà náà ni ĺrun wí pé, “Mo fi gbogbo ohun ̀gbìn tí ń so èso fún un yín bí oúnjẹ àti àwn igi eléso pẹ̀lú. Gbogbo rẹ̀ yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín.
31  GEN 1:31  ĺrun sì rí àwn ohun gbogbo tí ó dá, ó dára gidigidi. Àṣálẹ́ àti òwúr̀ sì jẹ́ j́ kẹfà.
32  GEN 2:1  Báyìí ni ĺrun parí dídá àwn ̀run àti ayé, àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀.
33  GEN 2:2  j́ keje ĺrun sì parí iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ti ń ṣe; ó sì sinmi ní j́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo tí ó ti ń ṣe.
34  GEN 2:3  ĺrun sì súre fún j́ keje, ó sì yà á sí míḿ, nítorí pé ní j́ náà ni ó sinmi kúrò nínú iṣẹ́ dídá ayé tí ó ti ń ṣe.
35  GEN 2:4  Èyí ni ìtàn bí ĺrun ṣe dá àwn ̀run àti ayé nígbà tí ó dá wn. Nígbà tí Olúwa ĺrun dá ayé àti àwn ̀run.
36  GEN 2:5  Kò sí igi igbó kan ní orí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ewéko igbó kan tí ó tí ì hù jáde ní ilẹ̀, nítorí Olúwa ĺrun kò tí ì r̀jò sórí ilẹ̀, kò sì sí ènìyàn láti ro ilẹ̀.
38  GEN 2:7  Olúwa ĺrun sì fi erùpẹ̀ ilẹ̀ m ènìyàn, ó si mí èémí ìyè sí ihò imú rẹ̀, ènìyàn sì di alààyè kàn.
39  GEN 2:8  Olúwa ĺrun sì gbin gbà kan sí Edeni ní ìhà ìlà-oòrùn, níbẹ̀ ni ó fi kùnrin náà tí ó ti dá sí.
40  GEN 2:9  Olúwa ĺrun sì mú kí onírúurú igi hù jáde láti inú ilẹ̀, àwn igi tí ó dùn ún wò lójú, tí ó sì dára fún oúnjẹ. Ní àárín gbà náà ni igi ìyè àti igi tí ń mú ènìyàn m rere àti búburú wà.
46  GEN 2:15  Olúwa ĺrun kùnrin náà sínú gbà Edeni láti máa ṣe iṣẹ́ níbẹ̀, kí ó sì máa ṣe ìt́jú rẹ̀.
47  GEN 2:16  Olúwa ĺrun sì pàṣẹ fún kùnrin náà pé, “Ìw lè jẹ lára èyíkéyìí èso àwn igi inú gbà;
49  GEN 2:18  Olúwa ĺrun wí pé, “Kò dára kí kùnrin wà ní òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànĺẃ tí ó rí bí i rẹ̀ fún un.”
50  GEN 2:19  Lẹ́yìn tí Olúwa ĺrun ti dá àwn ẹranko inú igbó àti gbogbo ẹyẹ ojú ̀run láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀. Ó sì kó wn t kùnrin náà wá láti wo orúk tí yóò s ẃn; orúk tí ó sì s gbogbo ẹ̀dá alààyè náà ni ẃn ń jẹ́.
52  GEN 2:21  Nígbà náà ni Olúwa ĺrun mú kí kùnrin náà sùn fnfn; nígbà tí ó sì ń sùn, ĺrun y egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà.
53  GEN 2:22  Olúwa ĺrun sì dá obìnrin láti inú egungun tí ó y ní ìhà kùnrin náà, Ó sì mu obìnrin náà t̀ ́ wá.
54  GEN 2:23  kùnrin náà sì wí pé, “Èyí ni egungun láti inú egungun mi àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi; ‘obìnrin’ ni a ó máa pè é, nítorí a mú un jáde láti ara kùnrin.”
56  GEN 2:25  kùnrin náà àti aya rẹ̀ sì wà ní ìhòhò, ojú kò sì tì ẃn.
57  GEN 3:1  Ejò sá à ṣe alárékérekè ju àwn ẹranko igbó yòókù tí Olúwa ĺrun l. Ó s fún obìnrin náà pé, “Ǹjẹ́ òtít́ ha ni ĺrun wí pé, ‘Ẹ̀yin kò gbd̀ jẹ èso èyíkéyìí lára àwn igi tí ó wà nínú gbà’?”
59  GEN 3:3  ṣùgb́n ĺrun s pé, ‘Ẹ̀yin kò gbd̀ jẹ lára èso igi tí ó wà láàrín gbà, ẹ kò sì gbd̀ fi ẃ kàn án, bí ẹ̀yin bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin yóò kùú.’ ”
61  GEN 3:5  “Nítorí ĺrun m̀ wí pé, bí ẹ̀yin bá jẹ nínú rẹ̀, ojú yín yóò là, ẹ̀yin yóò sì dàbí ĺrun, ẹ̀yin yóò sì m rere yàt̀ sí búburú.”
64  GEN 3:8  Nígbà náà ni kùnrin náà àti aya rẹ̀ gb́ ìró Olúwa ĺrun bí ó ti ń rìn nínú gbà, nígbà tí ojú j́ tura, ẃn sì fi ara paḿ kúrò níwájú Olúwa ĺrun sí àárín àwn igi inú gbà.
65  GEN 3:9  Ṣùgb́n Olúwa ĺrun ké pe kùnrin náà pé, “Níbo ni ìw wà?”
67  GEN 3:11  ĺrun wí pé, “Ta ni ó wí fún pé ìhòhò ni ìw wà? Ṣé ìw ti jẹ nínú èso igi tí mo pàṣẹ fún ìw gbd̀ jẹ nínú rẹ̀ ni?”
68  GEN 3:12  kùnrin náà wí pé, “Obìnrin tí ìw fi fún mi, ni ó fún mi nínú èso igi náà, mo sì jẹ ẹ́.”
69  GEN 3:13  Nígbà náà ni Olúwa ĺrun wí pé, “Èwo ni èyí tí ìw ṣe yìí?” Obìnrin náà dáhùn pé, “Ejò ni ó tàn mí jẹ, mo sì jẹ ẹ́.”
70  GEN 3:14  Nígbà náà ni Olúwa ĺrun wí fún ejò náà pé, “Nítorí tí ìw ti ṣe èyí, “Ègún ni fún ju gbogbo ohun ̀sìn àti gbogbo ẹranko igbó tókù l! Àyà rẹ ni ìw yóò fi máa ẃ, ìw yóò sì máa jẹ erùpẹ̀ ilẹ̀ ní gbogbo j́ ayé rẹ.
72  GEN 3:16  ĺrun wí fún obìnrin náà pé, “Èmi yóò fi kún ìrora rẹ ní àkókò ìbím; ni ìrora ni ìw yóò máa bí m. ̀d̀ k rẹ ni ìfẹ́ rẹ yóò máa fà sí, òun ni yóò sì máa ṣe àkóso rẹ.”
73  GEN 3:17  ĺrun sì wí fún Adamu pé, “Nítorí pé ìw fetí sí aya rẹ, ìw sì jẹ nínú èso igi tí mo pàṣẹ fún pé, ‘Ìw gbd̀ jẹ nínú rẹ̀,’ “Ègún ni fún ilẹ̀ nítorí rẹ; nínú ̀p̀ làálàá ni ìw yóò jẹ nínú rẹ̀, ní gbogbo j́ ayé rẹ.
77  GEN 3:21  Olúwa ĺrun, sì dá ẹ̀wù aw fún Adamu àti aya rẹ̀, ó sì fi ẁ ẃn.
78  GEN 3:22  Olúwa ĺrun sì wí pé,kùnrin náà ti dàbí ̀kan lára wa, ó m rere àti búburú. A kò gbd̀ jẹ́ kí ó na ẃ rẹ̀ kí ó mú lára èso igi ìyè kí ó sì jẹ, kí ó sì wà láààyè títí láéláé.”
79  GEN 3:23  Nítorí náà, Olúwa ĺrun lé e kúrò nínú gbà Edeni láti l máa ro ilẹ̀ nínú èyí tí a ti mú un jáde wá.
95  GEN 4:15  Ṣùgb́n, Olúwa wí fún pé, “Bẹ́ẹ̀ ḱ, bí ẹnikẹ́ni bá pa Kaini, èmi yóò gbẹ̀san ní ara onít̀hún ní ìgbà méje.” Nígbà náà ni ĺrun fi àmì sí ara Kaini, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ri má ba à pa á.
105  GEN 4:25  Adamu sì tún bá aya rẹ̀ lòp̀, ó sì bí mkùnrin kan tí ó pe orúk rẹ̀ ní Seti, tí ó túm̀ sí pé,ĺrun fún mi ní mkùnrin mìíràn ní ipò Abeli tí Kaini pa.”
107  GEN 5:1  Èyí ni àksílẹ̀ ìran Adamu. Nígbà tí ĺrun dá ènìyàn, ní àwòrán ĺrun ni ó dá a.
110  GEN 5:4  j́ Adamu, lẹ́yìn ìgbà tí ó bí Seti, jẹ́ ẹgbẹ̀rin (800) dún, ó sì bí àwn mkùnrin àti mbìnrin.
128  GEN 5:22  Lẹ́yìn tí ó bí Metusela, Enoku sì bá ĺrun rìn ní ̀́dúnrún (300) dún, ó sì bí àwn mkùnrin àti mbìnrin.
130  GEN 5:24  Enoku bá ĺrun rìn; a kò sì rí i ḿ nítorí ĺrun mú un l.
140  GEN 6:2  Àwn m ĺrun rí i wí pé àwn mbìnrin ènìyàn lẹ́wà, ẃn sì fẹ́ èyíkéyìí tí ó wù ẃn ṣe aya.
142  GEN 6:4  Àwn òmíràn wà láyé ní j́ ẁn-n-nì, àti lẹ́yìn ìgbà náà; nígbà tí àwn m ĺrun l àwn mbìnrin ènìyàn lòp̀ ẃn bím fún wn. Àwn náà ni ó di akni àti olókìkí ìgbà náà.
147  GEN 6:9  Ẁnyí ni ìtàn Noa. Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòót́ ènìyàn àti ẹni tí ó pé ní ìgbà ayé rẹ̀, ó sì fi òtít́ ĺrun rìn.
149  GEN 6:11  Ayé sì kún fún ìbàjẹ́ gidigidi ní ojú ĺrun, ó sì kún fún ìwà ipá pẹ̀lú.
150  GEN 6:12  ĺrun sì rí bí ayé ti bàjẹ́ tó, nítorí àwn ènìyàn inú ayé ti bá ara wn jẹ́ ní gbogbo ̀nà wn.
151  GEN 6:13  ĺrun sì wí fún Noa pé, “Èmi yóò pa gbogbo ènìyàn run, nítorí ilẹ̀ ayé kún fún ìwà ipá nípasẹ̀ wn. Èmi yóò pa ẃn run àti ayé pẹ̀lú.
160  GEN 6:22  Noa sì ṣe ohun gbogbo bí ĺrun ti pàṣẹ fún un.
169  GEN 7:9  ak àti abo ni ẃn wpẹ̀lú Noa sínú k̀ ĺrun ti pàṣẹ fún Noa.
176  GEN 7:16  Gbogbo ẃn w tak tabo bí ĺrun ti pàṣẹ fún Noa, Olúwa sì tì wn ḿ inú k̀.
185  GEN 8:1  ĺrun sì rántí Noa àti ohun alààyè gbogbo tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, bí àwn ẹranko igbó àti ohun ̀sìn, ó sì mú kí afẹ́fẹ́ fẹ́ sórí ilẹ̀, omi náà sì fà.
199  GEN 8:15  Nígbà náà ni ĺrun wí fún Noa pé.
207  GEN 9:1  ĺrun sì súre fún Noa àti àwn m rẹ̀ wí pé, “Ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì p̀ ní iye, kí ẹ sì kún ayé.
212  GEN 9:6  “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀, láti ẃ ènìyàn ni a ó gbà ta ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀. Nítorí ní àwòrán ĺrun ni ĺrun dá ènìyàn.
214  GEN 9:8  ĺrun sì wí fún Noa àti àwn m rẹ̀ pé,
218  GEN 9:12  ĺrun sì wí pé, “Èyí ni àmì májẹ̀mú tí mo ń dá yìí láàrín èmi àti ẹ̀yin àti ẹ̀dá alààyè tí ó wà pẹ̀lú yín, májẹ̀mú àtìrandíran tó ń b̀:
222  GEN 9:16  Nígbàkígbà tí òṣùmàrè bá y àwsánm̀, èmi yóò rí i, èmi yóò sì rántí májẹ̀mú ayérayé tí ń bẹ láàrín ĺrun àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń bẹ ní ayé.”
223  GEN 9:17  ĺrun sì wí fún Noa pé, “Èyí ni àmì májẹ̀mú tí mo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ láàrín èmi àti gbogbo alààyè ní ayé.”
232  GEN 9:26  Ó sì tún wí pé, “Olùbùkún ni Olúwa, ĺrun Ṣemu Kenaani yóò máa ṣe ẹrú fún Ṣemu.
233  GEN 9:27  ĺrun yóò mú Jafeti gbilẹ̀, Jafeti yóò máa gbé ní àǵ Ṣemu Kenaani yóò sì jẹ́ ẹrú fún un.”
277  GEN 11:10  Ẁnyí ni ìran Ṣemu. dún méjì lẹ́yìn ìkún omi, tí Ṣemu pé ǵrùn-ún dún ni ó bí Arfakṣadi.
354  GEN 14:17  Nígbà tí Abramu ti ṣẹ́gun Kedorlaomeri àti àwn ba tí ó pẹ̀lú rẹ̀, ba Sodomu l pàdé rẹ̀ ní àfonífojì Ṣafe (èyí ni àfonífojì ba).
355  GEN 14:18  Melkisedeki ba Salẹmu sì mú oúnjẹ àti wáìnì jáde wá. Òun ni àlùfáà ĺrun ̀gá-ògo.
356  GEN 14:19  Ó sì súre fún Abramu, wí pé, “Ìbùkún ni fún Abramu ti ĺrun ̀gá-ògo, Ẹni tí ó dá ̀run òun ayé.
357  GEN 14:20  Ìbùkún sì ni fún ĺrun ̀gá-ògo jùl, tí ó fi àwn ̀tá rẹ lé ĺẃ.” Abramu sì fún un ní ìdámẹ́wàá ohun gbogbo.
358  GEN 14:21  ba Sodomu sì wí fún Abramu pé, “Kó àwn ènìyàn mi fún mi, ṣùgb́n àwn ẹrù fún ara rẹ.”
359  GEN 14:22  Ṣùgb́n Abramu dá ba Sodomu lóhùn pé, “Mo ti búra fún Olúwa, ĺrun ̀gá-ògo, tí ó dá ̀run àti ayé, mo sì ti gb́ẃ sókè,
365  GEN 15:4  ̀r̀ Olúwa sì tún t̀ ́ wá pé,kùnrin yìí ḱ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ bí kò ṣe m ìw bí fúnra rẹ̀ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ.”
395  GEN 16:13  Ó sì pe orúk Olúwa tí o bá s̀r̀ ní, “Ìw ni ĺrun tí ó rí mi,” nítorí tí ó wí pé, “Mo ti ri ẹni tí ó rí mi báyìí.”
399  GEN 17:1  Ní ìgbà tí Abramu di ẹni ̀kàndínĺǵrùn-ún dún, Olúwa farahàn án, ó sì wí pé, “Èmi ni ĺrun alágbára, máa rìn níwájú mi, kí o sì jẹ́ aláìlábùkù.
401  GEN 17:3  Abramu sì dojúbolẹ̀, ĺrun sì wí fún un pé.
405  GEN 17:7  Èmi yóò sì gbé májẹ̀mú mi kalẹ̀ láàrín tèmi tìrẹ, ní májẹ̀mú ayérayé àti láàrín irú-m rẹ ní ìran-ìran wn, láti máa ṣe ĺrun rẹ àti ti irú-m rẹ lẹ́yìn rẹ.