Wildebeest analysis examples for:   yor-yor   N    February 11, 2023 at 20:00    Script wb_pprint_html.py   by Ulf Hermjakob

1  GEN 1:1  Ní ìbẹ̀rẹ̀ ohun gbogbo Ọlọ́run àwọn ọ̀run àti ayé.
21  GEN 1:21  Nítorí náà Ọlọ́run àwọn ẹ̀dá alààyè ńlá ńlá sí inú òkun, àwọn ohun ẹlẹ́mìí àti àwọn ohun tí ńn ní onírúurú tiwọn, àti àwọn ẹyẹ abìyẹ́ ní onírúurú tiwọn. Ọlọ́run sì rí i pé ó dára.
27  GEN 1:27  Nítorí náà, Ọlọ́run ènìyàn ní àwòrán ara rẹ̀, ní àwòrán Ọlọ́run ni ó dá a, akọ àti abo ni ó dá wọn.
29  GEN 1:29  Nígbà náà ni Ọlọ́run wí pé, “Mo fi gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ń so èson un n njẹ àti àwọn igi eléso pẹ̀lú. Gbogbo rẹ̀ yóò jẹ́njẹ n un n.
33  GEN 2:2  Ní ọjọ́ keje Ọlọ́run sì parí iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ti ń ṣe; ó sì sinmi ní ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo tí ó ti ń ṣe.
35  GEN 2:4  Èyí ni ìtàn Ọlọ́run ṣe dá àwọn ọ̀run àti ayé nígbà tí ó dá wọn. Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run dá ayé àti àwọn ọ̀run.
40  GEN 2:9  Olúwa Ọlọ́run sì mú kí onírúurú igi hù jáde láti inú ilẹ̀, àwọn igi tí ón ún wò lójú, tí ó sì dáran njẹ. Ní àárín ọgbà náà ni igi ìyè àti igi tí ń mú ènìyàn mọ rere àti búburú wà.
52  GEN 2:21  Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run mú kí ọkùnrin náà n fọnfọn; nígbà tí ó sì ńn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà.
55  GEN 2:24  Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò sì dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò sì di ara kan.
61  GEN 3:5  Nítorí Ọlọ́run mọ̀ wí pé, bí ẹ̀yin bá jẹ nínú rẹ̀, ojún yóò là, ẹ̀yin yóò sì dàbí Ọlọ́run, ẹ̀yin yóò sì mọ rere yàtọ̀ sí búburú.”
62  GEN 3:6  Nígbà obìnrin náà rí i wí pé èso igi náà dáran njẹ àti pé, ó sìn ún wò, àti pé ó ń mú ni ní ọgbọ́n, ó mú díẹ̀ níbẹ̀, ó sì jẹ ẹ́. Ó sì mú díẹ̀n ọkọ rẹ̀,ni tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, òun náà sì jẹ ẹ́.
63  GEN 3:7  Nígbà náà ni ojú àwọn méjèèjì sì là, wọ́n sì mọ̀ pé àwọn ní ìhòhò; wọ́n n ewé ọ̀pọ̀tọ́ pọ̀, wọ́n sì fi bo ara wọn.
64  GEN 3:8  Nígbà náà ni ọkùnrin náà àti aya rẹ̀ gbọ́ ìró Olúwa Ọlọ́run bí ó ti ńn nínú ọgbà, nígbà tí ojú ọjọ́ tura, wọ́n sì fi ara pamọ́ kúrò níwájú Olúwa Ọlọ́run àárín àwọn igi inú ọgbà.
65  GEN 3:9  Ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run ké pe ọkùnrin náà pé,Níbo ni ìwọ wà?”
69  GEN 3:13  Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run wí pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe yìí?” Obìnrin náà dáhùn pé, “Ejò ni ón mí jẹ, mo sì jẹ ẹ́.”
70  GEN 3:14  Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run n ejò náà pé,Nítorí tí ìwọ ti ṣe èyí, “Ègún ni n ọ ju gbogbo ohun ọ̀sìn àti gbogbo ẹranko igbó tókù lọ! Àyà rẹ ni ìwọ yóò fi máa wọ́, ìwọ yóò sì máa jẹ erùpẹ̀ ilẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
73  GEN 3:17  Ọlọ́run sì wín Adamu pé,Nítorí pé ìwọ fetí sí aya rẹ, ìwọ sì jẹ nínú èso igi tí mo pàṣẹn ọ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀,’ “Ègún ni n ilẹ̀ nítorí rẹ; nínú ọ̀pọ̀ làálàá ni ìwọ yóò jẹ nínú rẹ̀, ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
75  GEN 3:19  Nínú òógùn ojú rẹ ni ìwọ yóò máa jẹun títí tí ìwọ yóò fi padà sí ilẹ̀, nítorí inú ilẹ̀ ni a ti mú ọ jáde wá; erùpẹ̀ ilẹ̀ sá à ni ìwọ, ìwọ yóò sì padà di erùpẹ̀.”
79  GEN 3:23  Nítorí náà, Olúwa Ọlọ́run lé e kúrò nínú ọgbà Edeni láti lọ máa ro ilẹ̀ nínú èyí tí a ti mú un jáde wá.
85  GEN 4:5  ṣùgbọ́n Olúwa kò fi ojúrere wo Kaini àti ẹbọ rẹ̀. Nítorí náà inú Kaini gidigidi, ojú rẹ̀ sì fàro.
86  GEN 4:6  Nígbà náà ni Olúwa bi Kaini pé, “Èéṣe tí ìwọ ńnú? Èéṣe tí ojú rẹ sì fàro?
89  GEN 4:9  Nígbà náà ni Olúwa béèrè lọ́wọ́ Kaini pé,Níbo ni Abeli arákùnrin rẹ wà?” Ó sì dáhùn pé, “Èmi kò mọ ibi tí ó wà, èmí ha ń ṣe olùṣọ́ arákùnrin mi bí?”
95  GEN 4:15  Ṣùgbọ́n, Olúwa wín pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, bínikẹ́ni bá pa Kaini, èmi yóò gbẹ̀san ní ara onítọ̀hún ní ìgbà méje.” Nígbà náà ni Ọlọ́run fi àmì sí ara Kaini, nikẹ́ni tí ó bá ri má ba à pa á.
96  GEN 4:16  Kaini sì kúrò níwájú Olúwa, ó sì ń gbé ilẹ̀ Nodi ní ìhà ìlà-oòrùn Edeni.
102  GEN 4:22  Silla náà sì bí ọmọkùnrin tí ń jẹ́ Tubali-Kaini, tí ó ń rọ oríṣìíríṣìí ohun èlò láti ara idẹ àti irin. Arábìnrin Tubali-Kaini ni Naama.
107  GEN 5:1  Èyí ni àkọsílẹ̀ ìran Adamu. Nígbà Ọlọ́run ènìyàn, ní àwòrán Ọlọ́run ni ó dá a.
109  GEN 5:3  Nígbà tí Adamu dini àádóje ọdún, ó bí ọmọkùnrin kan tí ó jọ ọ́, tí ó jẹ́ àwòrán ara rẹ̀, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Seti.
112  GEN 5:6  Nígbà tí Seti pé àrùnlélọ́gọ́rùnn ọdún, ó bí Enoṣi.
115  GEN 5:9  Nígbà Enoṣi dini àádọ́rùnn ọdún ni ó bí Kenani.
118  GEN 5:12  Nígbà Kenani di àádọ́rin ọdún ni ó bí Mahalaleli.
121  GEN 5:15  Nígbà tí Mahalaleli pé ọmọ àrùnlélọ́gọ́ta ọdún ni ó bí Jaredi.
124  GEN 5:18  Nígbà tí Jaredi pé ọmọ ọgọ́jọ ọdún ó lé méjì ni ó bí Enoku.
127  GEN 5:21  Nígbà Enoku pé ọmọ ọgọ́ta ọdún ó lé márùn ni ó bí Metusela.
131  GEN 5:25  Nígbà tí Metusela pé igba ọdún n mẹ́tàlá ní o bí Lameki.
134  GEN 5:28  Nígbà tí Lameki pé ọdún méjìlélọ́gọ́sàn án ni ó bí ọmọkùnrin kan.
135  GEN 5:29  Ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Noa, ó sì wí pé, “Eléyìí ni yóò tù wá nínú ni iṣẹ́ àti làálàá ọwọ́ wa, nítorí ilẹ̀ tí Olúwa ti fi gégùn ún.”
136  GEN 5:30  Lẹ́yìn tí ó bí Noa, Lameki gbén ẹgbẹ̀ta ọdún n márùnn (595), ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin.
138  GEN 5:32  Lẹ́yìn Noa pé ọmọ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (500) ọdún ni ó bí Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
139  GEN 6:1  Nígbà ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí ní pọ̀ si ní orí ilẹ̀, wọ́n sí bí àwọn ọmọbìnrin.
141  GEN 6:3  Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Èémí ìyè tí mo mínú ènìyàn ní máa gbé inú ènìyàn títí láé, nítorí ẹran-ara sá à ni òun, ọgọ́fà ọdún ni ọjọ́ rẹ̀ yóò jẹ́.”
145  GEN 6:7  Nítorí náà, Olúwa wí pé, “Èmi yóò pa ènìyàn tí mo ti dá run kúrò lórí ilẹ̀, ènìyàn àti ẹranko, àti ohun tí ń rákò, àti ẹyẹ ojú ọ̀run, nítorí inú mi bàjẹ́ pé mo ti dá wọn.”
146  GEN 6:8  Ṣùgbọ́n, Noa rí ojúrere Olúwa.
147  GEN 6:9  Wọ̀nni ìtàn Noa. Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àtini tí ó pé ní ìgbà ayé rẹ̀, ó sì fi òtítọ́ bá Ọlọ́run n.
148  GEN 6:10  Noa sì bí ọmọkùnrin mẹ́ta, Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
151  GEN 6:13  Ọlọ́run sì wín Noa pé, “Èmi yóò pa gbogbo ènìyàn run, nítorí ilẹ̀ ayén n ìwà ipá nípasẹ̀ wọn. Èmi yóò pa wọ́n run àti ayé pẹ̀lú.
152  GEN 6:14  Nítorí náà fi igi ọ̀mọ̀ kan ọkọ̀, kí o sì yọ yàrá sí inú rẹ̀, kí o sì fi ọ̀dà ilẹ̀ rẹ́ ẹ tinú-tẹ̀yìn.
160  GEN 6:22  Noa sì ṣe ohun gbogbo bí Ọlọ́run ti pàṣẹn un.
161  GEN 7:1  Nígbà náà ni Olúwa wín Noa pé, “Wọ inú ọkọ̀ lọ ìwọ àti gbogbo ìdílé rẹ, nítorí ìwọ nìkan ni mo rí bí olódodo nínú ìran yìí.
164  GEN 7:4  Nítorí ní ọjọ́ méje sí ìhín, èmi yóò rọ òjò sórí ilẹ̀n ogójì ọ̀sán àti ogójì òru, èmi yóò sì pa gbogbo ohun alààyè tí mo ti dá run kúrò lórí ilẹ̀.”
165  GEN 7:5  Noa sì ṣe ohun gbogbo tí Olúwa pàṣẹn un.
166  GEN 7:6  Noa jẹ́ ọmọ ẹgbẹ̀ta (600) ọdún nígbà ìkún omi dé sórí ilẹ̀.
167  GEN 7:7  Noa àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn aya ọmọ rẹ̀ sì wọ inú ọkọ láti sá àsálàn ìkún omi.
169  GEN 7:9  akọ àti abo ni wọ́n wọlé pẹ̀lú Noa nú ọkọ̀ bí Ọlọ́run ti pàṣẹn Noa.
171  GEN 7:11  Ní ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kejì, tí Noa pé ọmọ ẹgbẹ̀ta (600) ọdún, ni gbogbo ìsun ibú ya, fèrèsé ìṣàn omi ọ̀run sì ṣí sílẹ̀.
173  GEN 7:13  Ní ọjọ́ tí ìkún omi yóò bẹ̀rẹ̀ gan an ni Noa àti Ṣemu, Hamu àti Jafeti pẹ̀lú aya Noa àti aya àwọn ọmọ rẹ̀ wọ inú ọkọ̀.
175  GEN 7:15  Méjì méjì ni gbogbo ẹ̀dá tí ó ní èémí ìyè nínú wọlé pẹ̀lú Noa nú ọkọ̀.
176  GEN 7:16  Gbogbo wọ́n wọlé ní takọ tabo bí Ọlọ́run ti pàṣẹn Noa, Olúwa sì tì wọn mọ́ inú ọkọ̀.
183  GEN 7:23  Gbogbo ohun alààyè tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé ni a parẹ́: ènìyàn àti ẹranko, àwọn ohun tí ńn nílẹ̀, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run pátápátá ló ṣègbé. Noa àti àwọn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ nínú ọkọ̀ ni ó ṣẹ́kù.
185  GEN 8:1  Ọlọ́run nNoa àti ohun alààyè gbogbo tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, bí àwọn ẹranko igbó àti ohun ọ̀sìn, ó sì mú kí afẹ́fẹ́ fẹ́ sórí ilẹ̀, omi náà sì fà.
188  GEN 8:4  Ní ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kejì ni ọkọ̀ náà nlẹ̀ sórí òkè Ararati.
189  GEN 8:5  Omi náà sì ń gbẹ si títí di oṣù kẹwàá. Ní ọjọ́nn-ní oṣù kẹwàá, orí àwọn òkè sì farahàn.
190  GEN 8:6  Lẹ́yìn ogójì ọjọ́, Noa sí fèrèsé tí ó ṣe sára ọkọ̀.
193  GEN 8:9  Ṣùgbọ́n àdàbà náà kò rí ìyàngbẹ ilẹ̀ bà lé nítorí omi kò tí ì tan lórí ilẹ̀, ó sì padà sọ́dọ̀ Noa. Noa na ọwọ́ rẹ̀ jáde ó sì mú ẹyẹ náà wọlé sọ́dọ̀ ara rẹ̀ nínú ọkọ̀.
195  GEN 8:11  Nígbà tí àdàbà náà padà sọ́dọ̀ rẹ̀ ní àṣálẹ́, ó já ewé igi olifi tútù hánu! Nígbà náà ni Noa mọ̀ pé omi ti ń gbẹ kúrò lórí ilẹ̀.
196  GEN 8:12  Noa n mú sùúrùn ọjọ́ méje, ó sìn n àdàbà náà jáde, ṣùgbọ́n àdàbà náà kò padà sọ́dọ̀ rẹ̀ mọ́.
197  GEN 8:13  Ní ọjọ́nn-ní oṣùnn-ní, ní ọdún kọ́kànlélẹ́gbẹ̀ta (601) ni omi náà gbẹ kúrò lórí ilẹ̀; Noa sì ṣí ọkọ̀, ó sì ri pé ilẹ̀ ti gbẹ.
198  GEN 8:14  Ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì, ilẹ̀ ti gbẹ pátápátá.
199  GEN 8:15  Nígbà náà ni Ọlọ́run n Noa pé.
202  GEN 8:18  Noa, àwọn ọmọ rẹ̀, aya rẹ̀ àti àwọn aya ọmọ rẹ̀ sì jáde.
204  GEN 8:20  Noa sì mọ pẹpẹn Olúwa, ó sì mú lára àwọn ẹran tí ó mọ́ àti ẹyẹ tí ó mọ́, ó sì fi rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ.
206  GEN 8:22  Níwọ́n ìgbà tí ayé bá sì wà, ìgbà ọ̀gbìn àti ìgbà ìkórè ìgbà òtútù àti ìgbà ooru, ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn àti ìgbà òjò, ìgbà ọ̀sán àti ìgbà òru, yóò wà títí láé.”
207  GEN 9:1  Ọlọ́run sì súren Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ wí pé, “Ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì pọ̀ ní iye, kí ẹ sìn ayé.
211  GEN 9:5  Nítòótọ́ ẹ̀jẹ̀n, àní ẹ̀mín, ni èmi yóò sì béèrè; lọ́wọ́ gbogbo ẹranko ni èmí yóò béèrè rẹ̀, àti lọ́wọ́ ènìyàn, lọ́wọ́ arákùnrin olúkúlùkù ènìyàn ni èmi yóò béèrè ẹ̀mí ènìyàn.
212  GEN 9:6  “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀, láti ọwọ́ ènìyàn ni a ó gbà ta ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀. Nítorí ní àwòrán Ọlọ́run ni Ọlọ́run ènìyàn.
214  GEN 9:8  Ọlọ́run sì wín Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé,
220  GEN 9:14  Nígbàkígbà tí mo bá mú kí òjò ṣú, tí òṣùmàrè bá farahàn ní àwọsánmọ̀.
222  GEN 9:16  Nígbàkígbà tí òṣùmàrè bá yọ ní àwọsánmọ̀, èmi yóò rí i, èmi yóò sìnmájẹ̀mú ayérayé tí ń bẹ láàrín Ọlọ́run àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń bẹ ní ayé.”
223  GEN 9:17  Ọlọ́run sì wín Noa pé, “Èyí ni àmì májẹ̀mú tí mo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ láàrín èmi àti gbogbo alààyè ní ayé.”
224  GEN 9:18  Àwọn ọmọ Noa tí ó jáde nínú ọkọ̀ ni Ṣemu, Hamu àti Jafeti. (Hamu ni baba Kenaani.)
225  GEN 9:19  Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Noa mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí ni gbogbo ènìyàn tin ká gbogbo ilẹ̀ ayé.
226  GEN 9:20  Noa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ àgbẹ̀, ó sì gbin ọgbà àjàrà.
230  GEN 9:24  Nígbà Noa kúrò ní ojú ọtí, tí ó sì mọ ohun tí ọmọ rẹ̀ kékeré ṣe sí i.
234  GEN 9:28  Noa wà láààyèn irinọdún n àádọ́ta (350) lẹ́yìn ìkún omi.
235  GEN 9:29  Àpapọ̀ ọjọ́ ayé Noa jẹ́ ẹgbẹ̀rún ọdún n làádọ́ta (950), ó sì kú.
236  GEN 10:1  Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
243  GEN 10:8  Kuṣi sì bí Nimrodu, ni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
244  GEN 10:9  Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
246  GEN 10:11  Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
247  GEN 10:12  àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
248  GEN 10:13  Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu.
267  GEN 10:32  Àwọn wọ̀nni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn tin ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.